Skip to content
Gẹnẹsisi 21:9-10

Gẹnẹsisi 21:9-10

9
Ṣùgbọ́n Sara rí ọmọ Hagari ará Ejibiti tí ó bí fún Abrahamu tí ó fi ṣe ẹlẹ́yà,
10
ó sì wí fún Abrahamu pé, “Lé ẹrúbìnrin yìí àti ọmọ rẹ̀ jáde, nítorí ọmọ ẹrú yìí kò ní bá ọmọ mi Isaaki pín ogún.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options