Skip to content
Daniẹli 9:1-2

Dáníẹ́lì Kẹ́kọ̀ọ́ Àsọtẹ́lẹ̀ Jeremáyà

Daniẹli 9:1-2
1
Ní ọdún kìn-ín-ní Dariusi ọmọ Ahaswerusi, ẹni tí a bí ní Media, òun ló jẹ ọba lórí ìjọba Babeli.
2
Ní ọdún kìn-ín-ní ìjọba rẹ̀, èmi Daniẹli fi iyè sí i láti inú ìwé, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa tí wòlíì Jeremiah, wá pé, àádọ́rin ọdún ni Jerusalẹmu yóò fi wà ní ahoro.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options