Skip to content
1 Ọba 2:10-11

1 Ọba 2:10-11

10
Nígbà náà ni Dafidi sinmi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín ní ìlú Dafidi.
11
Dafidi ti jẹ ọba lórí Israẹli ní ogójì ọdún, ọdún méje ni Hebroni àti ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n ní Jerusalẹmu.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options