Skip to content
Saamu 47:8-9

OLÚWA ń ṣàkóso lórí gbogbo orílẹ̀-èdè

Saamu 47:8-9
8
Ọlọ́run jẹ ọba lórí gbogbo kèfèrí; Ọlọ́run jókòó lórí ìtẹ́ ìwà mímọ́ rẹ̀.
9
Àwọn aládé ayé kó ara wọn jọ gẹ́gẹ́ bí ènìyàn Ọlọ́run Abrahamu nítorí asà ayé ti Ọlọ́run ni, òun ni ó ga jùlọ.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options