Skip to content
Saamu 116:18-19

Saamu 116:18-19

18
Èmi yóò mú ìlérí mi sẹ sí Olúwa ní ojú gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀,
19
nínú àgbàlá ilé Olúwa ní àárín rẹ̀, ìwọ Jerusalẹmu. Ẹ yin Olúwa.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options