Skip to content
Saamu 113:4-6

Saamu 113:4-6

4
Olúwa ga lórí gbogbo orílẹ̀-èdè, àti ògo rẹ̀ lórí àwọn ọ̀run.
5
Ta ló dàbí Olúwa Ọlọ́run wa, tí ó gbé ní ibi gíga.
6
Tí ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀ láti wò òun tí ó ń bẹ lọ́run, àti nínú ayé!
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options