Numeri 1:5-15
5
“Orúkọ àwọn ọkùnrin tí yóò ràn ọ́ lọ́wọ́ nìyí: “Láti ọ̀dọ̀ Reubeni, Elisuri ọmọ Ṣedeuri.
6
Láti ọ̀dọ̀ Simeoni, Ṣelumieli ọmọ Suriṣaddai.
7
Láti ọ̀dọ̀ Juda, Nahiṣoni ọmọ Amminadabu.
8
Láti ọ̀dọ̀ Isakari, Netaneli ọmọ Suari.
9
Láti ọ̀dọ̀ Sebuluni, Eliabu ọmọ Heloni.
10
Láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Josẹfu: láti ọ̀dọ̀ Efraimu, Eliṣama ọmọ Ammihudu. Láti ọ̀dọ̀ Manase, Gamalieli ọmọ Pedasuri.
11
Láti ọ̀dọ̀ Benjamini, Abidani ọmọ Gideoni.
12
Láti ọ̀dọ̀ Dani, Ahieseri ọmọ Ammiṣaddai.
13
Láti ọ̀dọ̀ Aṣeri, Pagieli ọmọ Okanri.
14
Láti ọ̀dọ̀ Gadi, Eliasafu ọmọ Deueli.
15
Láti ọ̀dọ̀ Naftali, Ahira ọmọ Enani.”
Settings