דלג לתוכן
Mika 7:15-16

Mika 7:15-16

15
“Bí i ọjọ́ tí ó jáde kúrò ní Ejibiti wá, ni èmi yóò fi ohun ìyanu hàn án.”
16
Orílẹ̀-èdè yóò rí i, ojú yóò sì tì wọ́n, nínú gbogbo agbára wọn. Wọn yóò fi ọwọ́ lé ẹnu wọn, etí wọn yóò sì di.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options