Skip to content
Luku 9:54-55

Luku 9:54-55

54
Nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ Jakọbu àti Johanu sì rí i, wọ́n ní, “Olúwa wa, jẹ́ kí a pe iná láti ọ̀run wá, kí a sì pa wọ́n run, bí Elijah ti ṣe?”
55
Ṣùgbọ́n Jesu yípadà, ó sì bá wọn wí.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options