Skip to content
Luku 2:41-42

Luku 2:41-42

41
Àwọn òbí rẹ̀ a sì máa lọ sí Jerusalẹmu ní ọdọọdún sí àjọ ìrékọjá.
42
Nígbà tí ó sì di ọmọ ọdún méjìlá, wọ́n gòkè lọ sí Jerusalẹmu gẹ́gẹ́ bí ìṣe àjọ náà.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options