Skip to content
Luku 13:10-12

Luku 13:10-12

10
Ó sì ń kọ́ni nínú Sinagọgu kan ní ọjọ́ ìsinmi.
11
Sì kíyèsi i, obìnrin kan wà níbẹ̀ tí ó ní ẹ̀mí àìlera, láti ọdún méjìdínlógún wá, ẹni tí ó tẹ̀ tán, tí kò le gbé ara rẹ̀ sókè bí ó ti wù kí ó ṣe.
12
Nígbà tí Jesu rí i, ó pè é sí ọ̀dọ̀, ó sì wí fún un pé, “Obìnrin yìí, a tú ọ sílẹ̀ lọ́wọ́ àìlera rẹ.”
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options