Skip to content
Onidajọ 17:5-6

Mika dá ibi ìbọ̀sìn tirẹ̀ sílẹ̀

Onidajọ 17:5-6
5
Ọkùnrin náà, Mika sì ní ojúbọ kan. Òun sì ra ẹ̀wù efodu kan, ó sì ṣe àwọn ère kan, ó sì fi ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin ṣe àlùfáà rẹ̀.
6
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ọmọ Israẹli kò ní ọba; olúkúlùkù ṣe bí ó ti rò pé ó tọ́ ní ojú ara rẹ́.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options