Skip to content
Johanu 16:8-11

Johanu 16:8-11

8
Nígbà tí òun bá sì dé, yóò fi òye yé aráyé ní ti ẹ̀ṣẹ̀, àti ní ti òdodo, àti ní ti ìdájọ́,
9
ní ti ẹ̀ṣẹ̀, nítorí tí wọn kò gbà mí gbọ́;
10
ní ti òdodo, nítorí tí èmi ń lọ sọ́dọ̀ Baba, ẹ̀yin kò sì mọ̀ mí.
11
Ní ti ìdájọ́, nítorí tí a ti ṣe ìdájọ́ ọmọ-aládé ayé yìí.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options