Skip to content
Johanu 15:1-3

Johanu 15:1-3

1
“Èmi ni àjàrà tòótọ́, Baba mi sì ni olùṣọ́gbà.
2
Gbogbo ẹ̀ka nínú mi tí kò bá so èso, òun a mú kúrò, gbogbo ẹ̀ka tí ó bá sì so èso, òun a wẹ̀ ẹ́ mọ́, kí ó lè so èso sí i.
3
Ẹ̀yin mọ́ nísinsin yìí nítorí ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ fún yín.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options