Skip to content
Jobu 40:1-5

Jobu 40:1-5

1
Olúwa dá Jobu lóhùn sí pẹ̀lú, ó sì wí pé,
2
“Ẹni tí ń bá Olódùmarè wíjọ́ yóò ha kọ ní ẹ̀kọ́? Ẹni tí ń bá Ọlọ́run wí jẹ́ kí ó dáhùn!”
3
Nígbà náà ni Jobu dá Olúwa lóhùn wá ó sì wí pé,
4
“Kíyèsi i, ẹ̀gbin ni èmi—ohun kí ni èmi ó dà? Èmi ó fi ọwọ́ mi le ẹnu mi.
5
Ẹ̀ẹ̀kan ní mo sọ̀rọ̀, ṣùgbọ́n èmi kì yóò tún sọ mọ́; lẹ́ẹ̀kejì ni, èmi kò sì le ṣe é mọ́.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options