Skip to content
Jeremiah 1:4-5

Jeremiah 1:4-5

4
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá, wí pé,
5
“Kí ó tó di pé mo dá ọ láti inú ni mo ti mọ̀ ọ́n, kí ó sì tó di pé a bí ọ ni mo ti yà ọ́ sọ́tọ̀. Mo yàn ọ́ gẹ́gẹ́ bí wòlíì fún àwọn orílẹ̀-èdè.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options