Skip to content
Heberu 4:9-11

Heberu 4:9-11

9
nítorí náà ìsinmi kan kù fún àwọn ènìyàn Ọlọ́run.
10
Nítorí pé ẹni tí ó ba bọ́ sínú ìsinmi rẹ̀, òun pẹ̀lú sinmi kúrò nínú iṣẹ́ tirẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run ti sinmi kúrò nínú iṣẹ́ tirẹ̀.
11
Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí á múra gírí láti wọ inú ìsinmi náà, kí ẹnikẹ́ni má ba à ṣubú nípa irú àìgbàgbọ́ kan náà.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options