Skip to content
Esteri 8:1-2

A Fún Esteri Ní Ọ̀rọ̀ Hamani; A Gbé Mordekai Ga

Esteri 8:1-2
1
Ní ọjọ́ kan náà ni ọba Ahaswerusi fún Esteri ayaba ní ilé e Hamani, ọ̀tá àwọn Júù. Mordekai sì wá síwájú ọba, nítorí Esteri ti sọ bí ó ṣe jẹ́ sí ọba.
2
Ọba sì bọ́ òrùka dídán an rẹ̀, èyí tí ó ti gbà lọ́wọ́ Hamani ó sì fi fún Mordekai, Esteri sì yàn án gẹ́gẹ́ bí olórí ilé e Hamani.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options