Skip to content
2 Kronika 3:1-2

Ìkọ́ tẹ́ńpìlì bẹ̀rẹ̀

2 Kronika 3:1-2
1
Nígbà náà, Solomoni bẹ̀rẹ̀ sí ní kọ́ ilé Olúwa ní Jerusalẹmu lórí òkè Moria, níbi tí Olúwa ti farahan baba a rẹ̀ Dafidi. Ní orí ilẹ̀ ìpakà Arauna ará Jebusi, ibi tí Dafidi pèsè.
2
Ó bẹ̀rẹ̀ sí kíkọ́ rẹ̀ ní ọjọ́ kejì oṣù kejì ní ọdún kẹrin ìjọba rẹ̀.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options