Skip to content
1 Samuẹli 17:10-11

1 Samuẹli 17:10-11

10
Nígbà náà Filistini náà wí pé, “Èmi fi ìjà lọ ogun Israẹli ní òní! Ẹ mú ọkùnrin kan wá kí ẹ sì jẹ́ kí a bá ara wa jà.”
11
Nígbà tí Saulu àti gbogbo àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ ọ̀rọ̀ Filistini, ìdààmú bá wọn.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options