1 Ọba 9:17-19
17
Solomoni sì tún Geseri kọ́, àti Beti-Horoni ìsàlẹ̀,
18
àti Baalati àti Tadmori ní aginjù, láàrín rẹ̀,
19
àti gbogbo ìlú ìṣúra tí Solomoni ní, àti ìlú kẹ̀kẹ́ rẹ̀, àti ìlú fún àwọn ẹlẹ́ṣin rẹ̀, àti èyí tí ó ń fẹ́ láti kọ́ ní Jerusalẹmu, ní Lebanoni àti ní gbogbo ilẹ̀ ìjọba rẹ̀ tí ó ń ṣe àkóso.