Skip to content
1 Ọba 17:2-4

1 Ọba 17:2-4

2
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Elijah wá pé,
3
“Kúrò níhìn-ín, kọjú sí ìhà ìlà-oòrùn, kí o sì fi ara rẹ pamọ́ níbi odò Keriti, tí ń bẹ níwájú Jordani.
4
Ìwọ yóò mu nínú odò náà, mo sì ti pàṣẹ fún àwọn ẹyẹ ìwò láti máa bọ́ ọ níbẹ̀.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options