Skip to content
1 Kronika 22:6-7

1 Kronika 22:6-7

6
Nígbà náà ó pe Solomoni ọmọ rẹ̀ ó sì sọ fun pé kí ó kọ́ ilé fún un Olúwa, Ọlọ́run Israẹli.
7
Dafidi sì wí fún Solomoni pé, “Ọmọ mi, mo sì ní-in ní ọkàn mi láti kọ́ ilé fún orúkọ Olúwa Ọlọ́run mi.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options