Skip to content
Saamu 92:6-7

Saamu 92:6-7

6
Òpè ènìyàn kò mọ̀ ọ́n, aṣiwèrè kò sì mọ̀ ọ́n,
7
nígbà tí àwọn ènìyàn búburú bá rú jáde bí i koríko àti gbogbo àwọn olùṣe búburú gbèrú, wọn yóò run láéláé.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options