Skip to content
Saamu 55:16-18

Saamu 55:16-18

16
Ṣùgbọ́n èmi pe Ọlọ́run; Olúwa yóò sì gbà mí.
17
Ní alẹ́, ní òwúrọ̀ àti ní ọ̀sán èmi sọkún jáde nínú ìpọ́njú, o sì gbọ́ ohùn mi.
18
Ó rà mí padà láìléwu kúrò nínú ogun tí ó dìde sí mi, nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ó dìde sí mi.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options