Skip to content
Saamu 48:4-5

Saamu 48:4-5

4
Nígbà tí àwọn ọba kógun jọ pọ̀, wọ́n jùmọ̀ ń kọjá lọ.
5
Wọn rí i, bẹ́ẹ̀ ni ẹnu sì yà wọ́n, a yọ wọ́n lẹ́nu, wọ́n yára lọ.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options