Skip to content
Òwe 2:6-7

Òwe 2:6-7

6
Nítorí Olúwa ni ó ń fún ni ní ọgbọ́n, láti ẹnu rẹ̀ sì ni ìmọ̀ àti òye ti ń wá.
7
Ó to ìgbàlà fún àwọn olódodo, Òun ni asà fún àwọn tí ń rìn déédé,
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options