Skip to content
Òwe 2:5-6

Òwe 2:5-6

5
Nígbà náà ni ìwọ yóò bẹ̀rù Olúwa, ìwọ yóò sì rí ìmọ̀ Ọlọ́run.
6
Nítorí Olúwa ni ó ń fún ni ní ọgbọ́n, láti ẹnu rẹ̀ sì ni ìmọ̀ àti òye ti ń wá.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options