Skip to content
Numeri 16:4-5

Numeri 16:4-5

4
Nígbà tí Mose gbọ́ èyí, ó dojúbolẹ̀,
5
Ó sì sọ fún Kora àti gbogbo ẹgbẹ́ rẹ̀ pé, “Ní ọ̀la ni Olúwa yóò fi ẹni tí í ṣe tirẹ̀ àti ẹni tó mọ́ hàn, yóò sì mú kí ẹni náà súnmọ́ òun. Ẹni tí ó bá yàn ni yóò mú kí ó súnmọ́ òun.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options