Skip to content
Luku 4:18-19

Luku 4:18-19

18
“Ẹ̀mí Olúwa ń bẹ lára mi, nítorí tí ó fi àmì òróró yàn mí láti wàásù ìyìnrere fún àwọn òtòṣì. Ó ti rán mi wá láti wàásù ìdásílẹ̀ fún àwọn ìgbèkùn, àti ìmúnríran fún àwọn afọ́jú, àti láti jọ̀wọ́ àwọn tí a pa lára lọ́wọ́,
19
láti kéde ọdún ojúrere Olúwa.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options