Skip to content
Luku 15:11-12

Luku 15:11-12

11
Ó sì wí pé ọkùnrin kan ní ọmọ méjì:
12
“Èyí àbúrò nínú wọn wí fún baba rẹ̀ pé, ‘Baba, fún mi ní ìní tí ó kàn mí.’ Ó sì pín ohun ìní rẹ̀ fún wọn.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options