Skip to content
Gẹnẹsisi 6:7-8

Gẹnẹsisi 6:7-8

7
Nítorí náà, Olúwa wí pé, “Èmi yóò pa ènìyàn tí mo ti dá run kúrò lórí ilẹ̀, ènìyàn àti ẹranko, àti ohun tí ń rákò, àti ẹyẹ ojú ọ̀run, nítorí inú mi bàjẹ́ pé mo ti dá wọn.”
8
Ṣùgbọ́n, Noa rí ojúrere Olúwa.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options