Skip to content
Eksodu 6:28-30

Eksodu 6:28-30

28
Nígbà tí Olúwa bá Mose sọ̀rọ̀ ni Ejibiti,
29
Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Èmi ni Olúwa. Sọ ohun gbogbo ti mo ti sọ fún ọ fún Farao ọba Ejibiti.”
30
Ṣùgbọ́n Mose sì wí ní iwájú Olúwa pé, “Níwọ́n ìgbà ti mo jẹ́ akólòlò, ọ̀nà dà ti Farao yóò ṣe fi etí sí mi?”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options