Skip to content
Eksodu 6:2-4

Eksodu 6:2-4

2
Ọlọ́run sì tún sọ fún Mose pé, “Èmi ni Olúwa.
3
Mo fi ara hàn Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu bí Ọlọ́run alágbára, ṣùgbọ́n nípa orúkọ mi Olúwa, Èmi kò fi ara mi hàn wọ́n.
4
Èmí sì tún fi ìdí májẹ̀mú mi múlẹ̀ pẹ̀lú wọn láti fún wọn ní ilẹ̀ Kenaani, ilẹ̀ tí wọn gbé gẹ́gẹ́ bí àjèjì.
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options