Aller au contenu
Deuteronomi 5:2-5

Deuteronomi 5:2-5

2
Olúwa Ọlọ́run wa bá wa dá májẹ̀mú ní Horebu.
3
Kì í ṣe àwọn baba wa ni Olúwa bá dá májẹ̀mú yìí bí kò ṣe àwa, àní pẹ̀lú gbogbo àwa tí a wà láààyè níbí lónìí.
4
Olúwa bá a yín sọ̀rọ̀ lójúkojú láàrín iná lórí òkè.
5
(Ní ìgbà yìí, mo wà láàrín ẹ̀yin pẹ̀lú Ọlọ́run láti sọ ọ̀rọ̀ Olúwa fún un yín torí pé ẹ̀rù Ọlọ́run ń bà yín, ẹ kò sì lè kọjá lọ sórí òkè.) Ó sì wí pé,
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Reading Width 45 chars

Options