Skip to content
2 Kronika 6:1-2

2 Kronika 6:1-2

1
Nígbà náà ni Solomoni wí pé, “Olúwa ti sọ wí pé òun yóò máa gbé nínú òkùnkùn tí ó ṣú biribiri;
2
ṣùgbọ́n èmi ti kọ́ tẹmpili dáradára fún ọ ibi tí ìwọ yóò máa gbé títí láé.”
Settings

Reading Style

Typeface

Font Size 19px

Options