Skip to content
1 Samuẹli 15:10-11

1 Samuẹli 15:10-11

10
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Samuẹli wá pé,
11
“Èmi káàánú gidigidi pé mo fi Saulu jẹ ọba, nítorí pé ó ti yípadà kúrò lẹ́yìn mi, kò sì pa ọ̀rọ̀ mi mọ́.” Inú Samuẹli sì bàjẹ́ gidigidi, ó sì ké pe Olúwa ní gbogbo òru náà.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options