Skip to content
1 Kọrinti 15:21-22

1 Kọrinti 15:21-22

21
Nítorí ìgbà tí ó jẹ́ pé nípa ènìyàn ní ikú ti wá, nípa ènìyàn ní àjíǹde òkú sì ti wá pẹ̀lú.
22
Nítorí bí gbogbo ènìyàn ti kú nínú Adamu, bẹ́ẹ̀ ní a ó sì sọ gbogbo ènìyàn dí alààyè nínú Kristi.
Settings

Reading style

Typeface

Font size 19px

Reading width 90 chars

Options